Buhari: Mo fẹ́ se sáà kejì lórí oyè
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 1
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti kéde pe òun fẹ́ ṣe ìjọba ni sáà kéjì.
Bashir Ahmad, tíí se òlùrànlọ́wọ́ fún ààrẹ lórí ẹ̀rọ áyélujará, ló fi ọ̀rọ̀ náà sọwọ si orí opó Twitter rẹ̀.
Lẹyín rẹ̀ ni gómìnà ìpinlẹ Kaduna, Nasir El'Rufai náà kéde ìròyìn náà lórí Facebook rẹ̀
Skip X post Warning: Third party content may contain adverts
Allow X content?
This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.
End of X post
A yóò máa mú èrò àwọn aaráàlú wá fún yín lórí ìgbésẹ̀ yìí tó bá yá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
Content is not available
{{rankTranslation}}