Obìnrin kan ń pa ẹgbèrún méjìdínlógójì Pọ́ùn lọ́sẹ̀ fún isó títa
Oríṣun àwòrán, Others
Stephaine Matto nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí iṣẹ́ àràmàǹdà tó yàn láàyò ẹgbẹ̀rún kan dọ́là ni òun ń ta ìgò isó kan.
Ó ṣàlàyé pé ọ̀pọ̀ ènìyàn tó ń tẹ̀lé òun lórí orí ẹ̀rọ ayélujára fún òun ní àǹfààní láti ní oníbàárà púpọ̀.
Stepahine Matto fi kun pé òun ń ta àádọ́ta ìgò isó lọ́sẹ̀ kan.
- Lẹ́yìn wákàtí mẹ́ta tí wọ́n kéde pé ìyá mi kú, ó tún mi ọwọ́ rẹ̀ ooo - Ọmọ Iyabo Oko
- Àrà mérìírí! Ìbejí tí a bí ní ọdun 2021 àti 2022 pẹ̀lú ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀dògún láàrin wọn
- Ta ni Oloye Lekan Balogun tí àwọn Ìgbìmọ̀ Afọbajẹ Ibadan fẹnukò pé òun ni Olubadan ilẹ̀ Ibadan kàn?
- Afenifere, PDP, Ohaneze sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Buhari lórí ọ̀rọ̀ tó sọ nípa ètò ààbò
- Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti wẹ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ márùn-ún àti òṣìṣẹ́ márùn-ún ilé ẹ̀kọ́ Dowen College mọ́
Ẹwẹ̀, Stephaine ṣeéṣe kí isó tí ó ti fún kúrò lára pọ̀ púpọ̀ jù bí ó ṣe yẹ lo fi di èrò ilé ìwòsàn.
Ó ní ọ̀pọ̀ ẹ̀wà ni òun jẹ kí òun lè bá à máa rí isó ya ṣùgbọ́n ó ṣe àkóbá fún èèmí òun tí òun rò wí pé òun ti ní síròkì to jẹ arun rọpa rọsẹ.
Dókítà ti ní kí ó pààrọ̀ òunjẹ rẹ̀ báyìí kí àlááfìà le ba Stephaine.
Stephaine Matto ní ohun tí dókítà tí mú òpin bá iṣẹ́ òun ìpinnu tó dùn mọ́ àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ̀.
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
Content is not available
{{rankTranslation}}