Àṣìlò òògùn: Ará ìlú sọ oun tó ń sún wọn dé'dí ìwà yí
Oríṣun àwòrán, Guardian Nigeria
Awọn oniṣegun oyinbo ti n bẹnu atẹ lu aṣilo oogun lati ọjọ to ti pẹ, ṣugbon awọn ara ilu to ba ikọ BBC sọrọ ni wahala ti oju awọn n ri ti wọn ba lọ ile iwosan lo faa ti awọn fi di ẹni to n ṣi oogun lo.
Awọn oniṣegun oyinbo ti n bẹnu atẹ lu aṣilo oogun lati ọjọ to ti pẹ, ṣugbon awọn ara ilu to ba ikọ BBC sọrọ ni wahala ti oju awọn n ri ti wọn ba lọ ile iwosan lo faa ti awọn fi di ẹni to n ṣi oogun lo.
Awọn oniṣegun meji, Dokita Yetunde Adeniyi ati dokita Tope Ojo fesi si ọrọ yii, wọn ni, bo ti lẹ jẹ pe nitootọ ni pe oun ti oju ara ilu n ri lati gba iwosan ni awọn ile iwosan ko rọrun, ọpọlọpọ ewu lo wa nidi aṣilo oogun.
Àwọn iroyin miiran ti é le nifẹ si:
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
Content is not available
{{rankTranslation}}