Lassa Fever: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀
Lori eto Laahanmi ti BBC Yoruba, a se atupalẹ ohun ti iba Lassa jẹ, ọsẹ to n se lawujọ wa ati awọn ọna ta fi lee dena rẹ.
Fidio naa Laahanmi naa ree:
Iwadi fi ye wa pe awọn ekute ile lo n fa iba yii, eyi to n sekupa ọpọ eeyan lọwọlọwọ bayii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀
- Ẹ wo bí Amotekun ṣe gba ilẹ̀ Yoruba silẹ̀ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀ní ní igba ọdún sẹ́yìn
- Tí ìjọbá bá kọ̀ láti san owó oṣù wa, a o da iṣẹ́ sílẹ̀ - ASUU
- Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he
- Wo ìgbésẹ̀ tó yẹ ko gbé tí kokoro bá ba irè oko rẹ jẹ́
Ẹ wo fidio yii lati mọ iye eeyan ti arun yii ti pa, awsn ohun to n sokunfa rẹ, ami ta fi mọ pe iba Lassa wa lara eeyan kan ati ọna ta lee gba dena rẹ.
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
Content is not available
{{rankTranslation}}