You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
INEC ṣe àyípadà orúkọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ PDP sí ti igun Wike dìbò yàn lópin ọ̀sẹ̀
Àwọn aṣojú tí iye wọn tó 2,500 tó kópa níbi àpérò náà ló fẹnukò láti gbé àwọn aláṣẹ tuntun náà wọlé láì ṣe ètò ìdìbò kankan gẹ́gẹ́ bí ẹgbẹ́ náà ti ṣáájú kéde pé ìlànà fífi ẹnu kò lórí àwọn olùdíje ni àwón máa ṣe dípò ṣíṣe ètò ìdìbò.
Fídíò, "Mo ra ‘Sim Card’ táwọn ajínigbé ti fi gbá owó ìtúsílẹ̀ N50m, pa ẹni tí wọn jí gbé, mo bá dèrò àtìmọ́lé", Duration 4,32
Omidan Titilayo Ibrahim tí orí kó yọ lọ́wọ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn àti ìjínigbé ṣàlàyé ohun tí ojú rẹ̀ rí lọ́wọ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn àìmọ̀dí náà.
Kí ló fà á tí Funke Akindele kò fi dáhùn kíkí tí Toyin Abraham kí i lóde?
Bi fidio ọhun ṣe han to, ti ohun to ṣẹlẹ nibẹ ko ruju rara, aṣiri ohun to fa a ti Funke Akindele fi leju pa ko ti I han sita.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 0,59
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Agbèbọ́n tún ṣọṣẹ́ ní Plateau, pa ọ̀pọ̀ èèyàn lọ́jọ́ Ìsinmi Ọ̀pẹ
Ilu kan ti wọn n pe ni Gari Ya Waye, lagbegbe Angwan Rukuba, ipinlẹ Plateau ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Àjọ̀dún Lisabi 2026 gbọ̀rẹ̀gẹ̀jigẹ̀ lóòótọ́, àmọ́, a ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mẹ́yẹ bọ̀ lápò ni - Amosun
Liṣabi ni jagunjagun to lewaju awọn Ẹgba kuro niluu Oyo lọdun 1830 lati tẹdo si abẹ Olumo.
Wo ohun tó mú àyájọ́ ọjọ́ ìsinmi 'Palm Sunday' yàtọ̀
Ayajọ yii jẹ ọjọ ti awọn ọmọlẹyin Kristi fi maa n ṣe ami bi Jesu Kristi ṣe gun kẹtẹkẹtẹ wọ Jerusalem nigba to fi wa laye.
Lẹ́yìn ìpàdé àpapọ̀ l'Abuja, wo àwọn tí yóó tukọ̀ APC fọ́dún mẹ́rin
Nibi ipade ọhun ni wọn tun ti yan Alaga apapọ wọn, Nentawe Yilwatda ati Ajibola Basiru pada sipo alaga ati Akọwe apapọ ẹgbẹ APC.
Rògbòdìyàn PDP: Wo àwọn tọ kọ̀yìn sí ìpàdé àpapọ̀ igun Wike tí yóò wáyé l'Abuja lónìí
Pẹlu bi ẹgbẹ PDP ṣe ti pin, ti awọn alaga ẹgbẹ ti ṣe ọtọọtọ, ti ọpọ gomina PDP si ti kuro nibẹ, awọn kan ti sọ pe awọn ko ni i de ibi ipade ti Wike atawọn eeyan rẹ gbe kalẹ yii.
Afẹ́fẹ́ òjò fa ìjàmbá ọkọ̀ ńlá l'Osogbo
Ni deede aago mẹjọ alẹ ọjọ Àbámẹ́ta naa ni ojo to mu afẹfẹ nla dani naa rọ to si ba ọpọlọpọ nnkan jẹ niluu Osogbo.
Agbébọn 38 pàdé ikú lọ́wọ́ ológun Naijiria, wọ́n gba ìbọn AK-47 àti àdó olóró lọ́wọ́ wọn
Ikọ ti a tun a mọ si Operation Hadin Kai naa sọ pe owurọ kutu ọjọ Satide, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kẹta ọdun 2026 yii ni awọn mu awọn eeyan naa balẹ.
Agbébọn tó kó òṣìṣẹ́ mẹ́ta lọ nílé ìwòsàn l'Ondo, ohun tí a mọ̀ rèé
Awọn agbebọn naa ya wọ ile iwosan ọhun ni deede aago meji oru ọjọ Abamẹta, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kẹta ọdun 2026 yii, wọn si ko awọn osisẹ ibẹ mẹta lọ.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Yilwatda wọlé padà bíi Alága àpapọ̀ APC pẹ̀lú àwọn olóyè ẹgbẹ́
Bi wọn ṣe fẹnuko naa ni wọn si bura fun awọn alakoso tuntun yii lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀.
'Ìwà ọ̀daràn sí ẹ̀tọ́ ọmọnìyan tó burú jùlọ': Ṣé ó yẹ káwọn orílẹ̀ èdè tó kó ilẹ̀ Africa san owó gbà mábinú?
Igbimọ aṣofin aajọ ìṣọkan agbaye ti buwọlu kikede fifi awọn eeyan ṣe ẹru gẹgẹ bi iwa ọdaran to buru julọ ti wọn ṣe lati fi tẹ ẹtọ awọn eeyan mọlẹ. Nibi ifẹnuko naa ti wọn ti rọ gbogbo awọn orilẹ ede to ko awọn eeyan lẹru lati da awọn ohun ini awọn eeyan bẹẹ ti wọn ji ko pada.
Wo bí Naijiria, Egypt ṣe ń pàdánù lẹ́ka epo nítorí ogun Iran, tí nǹkan sì ń ṣe ẹnu ire fún South Africa
Ogun Iran mu ayipada ba iye owo epo ati bi wọn ṣe n gbe epo wọlu, o ko Naijiria ati Egypt ni papamọra ṣugbọn o n la ọna miran ti wọn le gba nipasẹ South Africa.
Ayẹyẹ ọdún Lisabi gbérasọ ní ìlú Abeokuta pẹ̀lú àwọn àkọ̀tun àrà
Bo tilẹ jẹ pe lati ọjọ Aje, ọsẹ yii, ni ayẹyẹ naa ti bẹrẹ pẹlu oniruuru eto ọlọkan-o-jọkan ti wọn ti la kalẹ, ṣugbọn oni ọjọ Abamẹta, ọjọ Kejidinlọgbọn, oṣu Kẹta ni aṣekagba eto naa, nibi ti awọn eeyan pataki ti wọn ti ṣe bẹbẹ ni oniruuru ẹka ti peju lati kopa.
ICPC tú El-Rufai sílẹ̀ lẹ́yìn tó pàdánù ìyá rẹ̀
Èyí ló ń wáyé lẹ́yìn tí ìròyìn gbòde pé El-Rufai pàdánù ìyá rẹ̀, Hajiya Umma El-Rufai ní ọjọ́ Ẹtí ní ìlú Cairo, orílẹ̀ èdè Egypt.
Ìyá tó bí ìbaàrún ní ìpínlẹ̀ Kano jáde láyé
Ọkunrin mẹta ati obinrin meji lawọn ibarun-un naa ti Eleduwa fi jinki Hafsatu Yusuf, nile iwosan Murtala Specialist hospital lo bi awọn ọmọ naa si ni Kano.
Iran tako ìgbésẹ Amẹrika láti parí ogun tó ń lọ, sọ nǹkan márùn ún tó lè mú wọn dá ogun dúró
Ṣaaju ni Iran ti sọ pe irọ nla lọrọ ti Aarẹ Donald Trump sọ pe Amẹrika ti n jiroro pẹlu Iran lati pari ogun naa.
Àwa là ń fiyà jẹ ara wa - Okunnu bu ẹnu àtẹ́ lu àwón alágbàtà epo bí owó bẹntiróòlù ṣe gbẹ́nu sókè
Okunnu ní ṣé ìjọba nìkan ló yẹ kí àwọn èèyàn máa báwí lórí ọ̀rọ̀ epo, pé ohun táwọn alágbàtà epo ń ṣe nínú gbogbo ọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀ yìí náà pọ̀.
Senegal yóò ṣàfihàn Ife ẹ̀yẹ AFCON 2025 lópin ọ̀sẹ̀ yìí, bó tilẹ̀ jẹ́ pé CAF ti gbé ife náà fún Morocco
Lọjọ Aabamẹta ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kẹta yii ni Senegal yoo ṣafihan ife ẹyẹ naa ki ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ ti wọn fẹ gba pẹlu Peru niluu Paris to bẹrẹ.
Àwọn agbébọn kọlu àwọn to ń gbé òkú lọ itẹ́ ní Kwara, yìnbọn pa fijilanté méjì, jí ọ̀kadà àti ìbọn wọn lọ
Lasiko tawọn fijilanté kan lọ ṣe aabo fun awọn to n gbe oku lati ilu Ilorin lọ si ilu Oke-Oyan ni ijọba ibilẹ Ifelodun fun eto isin idagbere la gbọ wi pe awọn agbebọn kọlu wọn, ti wọn si gbẹmi eeyan meji ninu wọn.
Ìdí tí mi ò ṣe kí ń lo ọkọ mi ṣùgbọ́n tí mo máa ń lo ọmọ mi nínú fídíò àwàdà tí mò ń ṣe rèé - Kiekie
Adẹrinpoṣonu naa sọ pe oun mọọmọ fi aala saarin iṣẹ toun n ṣe ati igbe aye toun n gbe ni.
Ìròyìn Pàtàkì
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Mo tọrọ àforíjì lọ́wọ́ ẹ̀yin ọmọ Naijiria fún iná ọba tí kò sí lásìkò yìí- Adelabu
Adelabu ṣo pe oun paapaa mọ pe ai si ina ọba deede yii n ṣe akoba pupọ fun ọrọ aje awọn eeyan, ka ma ti i sọ ti ooru buruku to n mu lasiko yii lai ṣiwọ.
Èmi ṣì ni alága NURTW- MC Oluomo
Ṣáájú ni ìròyìn tí kọ́kọ́ gbòde pé Baruwa àti àwọn èèyàn rẹ̀ yawọ ilé ẹgbẹ́ NURTW tó wà ní Abuja tí wọ́n sì fẹ́ àkóso ilé ẹgbẹ́ náà pé òun ni ilé ẹjọ́ dájọ́ pé òun ó jẹ́ ojúlówó alága ẹgbẹ́ náà.
Ohun tó máa ṣẹlẹ̀ sí ẹni tí kò bá dìbò fún Tinubu lọ́dún 2027 rè é - Portable
Nínú fídíò kan tí akọrin náà gbé sójú òpó Instagram rẹ̀ ló ti ń sọ àwọn ọ̀rọ̀ àlùfàńṣà, tó sì ń sọ̀rọ̀ sí àwọn tí kò bání dìbò fún Tinubu lọ́dún 2027.
'Biola Bayo, mo fà ẹ́ sí kóòtù Ọlọ́run'-Princess bú sígbe torí Baba Ijesa tí Biola Bayo gbé wá sóri ètò
Lori ifọrọwerọ naa ni Princess fi tun sọ pe Ọlọrun yoo ṣedajọ fun Biola ati Ijesa, to ba jẹ pe bi eeyan ṣe n ṣe ni wọn ṣe yẹn.
NBA,Ẹgbẹ́ Amòfin Naijiria bínú sí Sowore tó pàtẹ ìpàdé akọ̀ròyìn nínú kóòtù
Ilu Abuja ni iṣẹlẹ naa ti waye lanaa ọjọ Iṣẹgun, nile ẹjọ giga kan.
À n ṣiṣẹ́ kárakára láti dáàbò bò àwọn èèyàn Kwara- Kọmiṣọnna ọlọ́pàá Kwara
Olori ọdọ ilu naa, Baloude Najeem ti BBC Yoruba ba sọrọ lori ago sọ pe nnkan bi aago mẹjọ aarọ ni iṣẹlẹ naa waye.
Ìdí rèé tí àpapọ̀ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC, TUC, NULGE àti JNC fi fagilé ìfẹ̀họ́núhàn tí wọ́n fẹ́ ṣe tako bánkì UBA l'Osun
Lọsẹ to kọja ni awọn agbarijọpọ ẹgbẹ oṣiṣẹ ipinlẹ Osun ti kede pe ifẹhonuhan naa yoo waye ni ọjọ kẹrinlelogun osu yii lori bi ile ifowopamọ UBA ṣe kọ lati gbẹsẹ kuro lori owo ijọba ibilẹ to wa ni akata wọn.