Coronavirus in Nigeria: Ààrùn Covid-19 ti ran ènìyàn 454 míràn ní Nàìjíríà

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 40

Awọn eeyan mẹrinlelaadọta o le ni irinwo tuntun ni ajọ NCDC to n mojuto itankalẹ ajakalẹ arun ni Naijiria fi sita lalẹ ana ọjọ Ẹti, Ọjọ kẹta, Oṣu keje, ọdun 2020 pe wọn ṣẹṣe lugbadi Covid 19.

Bi akọsilẹ naa ṣe lọ niyii pẹlu ipinlẹ kọọkan ti wọn ti ri awọn eeyan naa

Lagos-87

Edo-63

FCT-60

Ondo-41

Benue-32

Abia-31

Ogun-29

Oyo-19

Kaduna-17

Delta-16

Enugu-15

Borno-14

Plateau-9

Nasarawa-8

Kano-5

Bauchi-4

Gombe-2

Katsina-1

Kogi-1

Titi di oni, ọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrin, oṣu keje, ọdun 2020, iye awọn to ti lugbadi Covid 19 ni Naijiria lapapọ jẹ 27,564.

Awọn to ti ri iwosan ti wọn ti pada sile wọn jẹ: 11,069.

Awọn to ti doloogbe si jẹ 628

Àjọ NCDC kéde ènìyàn 626 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà

Eeyan 626 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 27,110 bayii.

Eeyan 10,801 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 616 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-193

FCT-85

Oyo-41

Edo-38

Kwara-34

Abia-31

Ogun-29

Ondo-28

Rivers-26

Osun-21

Akwa Ibom-18

Delta-18

Enugu-15

Kaduna-13

Plateau-11

Borno-8

Bauchi-7

Adamawa-5

Gombe-4

Sokoto-1

Eeyan 790 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 26,484 bayii.

Eeyan 9,746 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 590 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Delta-166

Eko-120

Enugu-66

FCT-65

Edo-60

Ogun-43

Kano-41

Kaduna-39

Ondo-33

Rivers-32

Bayelsa-29

Katsina-21

Imo-20

Kwara-18

Oyo-11

Abia-10

Benue-6

Gombe-4

Yobe-2

Bauchi-2

Kebbi-2

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Eeyan 561 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 25,694 bayii.

Eeyan 9,746 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 590 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-200

Edo-119

Kaduna-52

FCT-52

Niger-32

Ogun-19

Ondo-16

Imo-14

Plateau-11

Abia-8

Oyo-8

Bayelsa-7

Katsina-6

Kano-5

Bauchi-3

Osun-3

Kebbi-3

Borno-2

Jigawa-1

Eeyan 566 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 25,133 bayii.

Eeyan 9,402 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 573 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-166

Oyo-66

Delta-53

Ebonyi-43

Plateau-34

Ondo-32

FCT-26

Ogun-25

Edo-24

Imo-15

Bayelsa-13

Benue-12

Gombe-11

Kano-11

Kaduna-11

Osun-8

Nasarawa-7

Borno-5

Katsina-2

Anambra-2

Eeyan 490 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 24,567 bayii.

Eeyan 9,007 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 565 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-118

Delta-84

Ebonyi-68

FCT-56

Plateau-39

Edo-29

Katsina-21

Imo-13

Ondo-12

Adamawa-11

Osun-8

Ogun-8

Rivers-6

Kano-5

Enugu-3

Bauchi-3

Akwa Ibom-3

Kogi-1

Oyo-1

Bayelsa-1

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Eeyan 779 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 24,077 bayii.

Eeyan 8,253 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 554 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-285

Rivers-68

FCT-60

Edo-60

Enugu-56

Delta-47

Ebonyi-42

Oyo-41

Kaduna-19

Ogun-18

Ondo-16

Imo-12

Sokoto-11

Borno-9

Nasarawa-8

Abia-5

Gombe-5

Kebbi-5

Kano-4

Yobe-3

Ekiti-3

Osun-2

Eeyan 684 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 23,298 bayii.

Eeyan 8,253 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 554 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-259

Oyo-76

Katsina-69

Delta-66

Rivers-46

Ogun-23

Edo-22

Osun-22

Ebonyi-21

FCT-20

Kaduna-16

Ondo-10

Imo-9

Abia-9

Gombe-5

Plateau-4

Bauchi-4

Ekiti-2

Anambra-1

Eeyan ẹgbẹtadinmẹfa lo tun ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.

Ajọ NCDC to fi ikede naa sita sọ pe eeyan 159 lo ni, nipinlẹ Eko, 106 si ni nipinlẹ Delta.

Esi ayẹwo to ku niyii:

Skip X post, 1
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 1

Oríṣun àwòrán, Ncdc

Àjọ NCDC kéde ènìyàn 649 tó tún ní Coronavirus ní Nàìjíríà ní 24/06/2020

Awọn to ni aarun Covid-19 ni Naijiria ti pe ẹgbẹrun mejilelogun (22,020) bayii.

Eyi ribẹ lẹyin ti ajọ NCDC tun kede eniyan 649 to tun ṣẹṣẹ ni aarun naa.

Ipinlẹ Eko lo ṣiwaju pẹlu 250, Oyo si tẹle pẹlu 100.

Skip X post, 2
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 2

Ajọ NCDC kede eniyan 452 ti ayẹwo fihan pe o ni Covid-19 ni 23/06/2020

jọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede eeyan 452 miran to ni aarun coronavirus ni Naijiria.

Eyi si ti mu ki apapọ awọn to ti ràn ni Naijiria o pe 21,371 bayii.

Akojọpọ iye awọn to ni niyii:

Skip X post, 3
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 3

Aarun naa ti pa eniyan 533, awọn 7,338 si ti ri iwosan.

Ènìyàn 675 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó ní Covid-19 ní Nàìjíríà ní 22/06/2020

Ajọ NCDC kede pe eniyan 675 ni esi ayẹwo tun fihan pe o ti ni coronavirus ni Naijiria.

Ipinlẹ Eko ni 288, Oyo si tẹle pẹlu 76.

Awọn to ku ni:

Rivers-56

Delta-31

Ebonyi-30

Gombe-28

Ondo-20

Kaduna-20

Kwara-20

Ogun-17

FCT-16

Edo-13

Abia-10

Nasarawa-9

Imo-9

Bayelsa-8

Borno-8

Katsina-8

Sokoto-3

Bauchi-3

Plateau-2

Lọwọlọwọ, o ti pe eniyan 20,919 to ti ni aarun naa.

Eniyan 436 lo ni aarun Covid-19 ni Naijiria ni 21/06/2020

Awọn ti ajakalẹ aarun coronavirus ti kọlu ni Naijiria ti pe 20,244 bayii.

Eyi ri bẹ lẹyin ti ajọ NCDC tun kede eniyan 436 to tun ṣẹṣẹ ni i lọjọ Aiku.

Esi ipinlẹ kọọkan re e:

Skip X post, 4
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 4

Eniyan 6,879 ti ri iwosan, ti 518 si ti ku.

Esi ayẹwo coronavirsu fun 20/06/2020

Diẹ lo ku ki awọn to ni aarun Covid-19 o pe ẹgbẹrun lọna ogun bayii, lẹyin ti ajọ to n mojuto aarun ni Naijiria, NCDC tun kede eniyan 661 lọjọ Abamẹta.

Lọwọlọwọ, eniyan 19,808 lo ti ni, 6,718 ti ri iwosan, awọn 506 si ti ku.

Bi akojọpọ esi ayẹwo tuntun naa ṣe lọ niyii:

Lagos-230

Rivers-127

Delta-83

FCT-60

Oyo-51

Edo-31

Bayelsa-27

Kaduna-25

Plateau-13

Ondo-6

Nasarawa-3

Ekiti-2

Kano-2

Borno-1

Eeyan 667 tuntun mii ni ajọ NCDC kede pe o ni arun Coronavirus ni Naijiria lọjọ Ẹti.

NCDC ni apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 19,147bayii.

Eeyan 6,581 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 487 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko -281

Abia-48

Oyo-45

FCT-38

Ogun-37

Enugu-31

Ondo-23

Plateau-21

Edo-19

Delta-18

Rivers-18

Bayelsa-17

Akwa Ibom-17

Kaduna-14

Kano-12

Bauchi-9

Gombe-4

Osun-3

Benue-3

Nasarawa-3

Kwara-3

Ekiti-2

Borno-1

Èèyàn 745 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀

Oríṣun àwòrán, Others

Eeyan 745 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 18,480 bayii.

Eeyan 6,307 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 475 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-280

Oyo-103

Ebonyi-72

FCT-60

Imo-46

Edo-34

Delta-33

Rivers-25

Kaduna-23

Ondo-16

Katsina-12

Kano-10

Bauchi-8

Borno-7

Kwara-5

Gombe-4

Sokoto-2

Enugu-2

Yobe-1

Osun-1

Nasarawa-1

Eeyan 587 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Oríṣun àwòrán, Others

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,658 bayii.

Eeyan 5,967 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 469 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-155

Edo-75

FCT-67

Rivers-65

Oyo-56

Delta-50

Bayelsa-25

Plateau-18

Kaduna-18

Enugu-17

Borno-12

Ogun-12

Ondo-7

Kwara-4

Kano-2

Gombe-2

Sokoto-1

Kebbi-1

Eeyan 490 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,658 bayii.

Eeyan 5,623 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 455 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-142

FCT-60

Bayelsa-54

Rivers-39

Delta-37

Oyo-30

Kaduna-26

Imo-23

Enugu-19

Kwara-17

Gombe-11

Ondo-10

Bauchi-8

Ogun-7

Borno-6

Benue-1

Èèyàn 573 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Aje

Eeyan 573 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,658 bayii.

Eeyan 5,349 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 424 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-216

Rivers-103

Oyo-68

Edo-40

Kano-21

Gombe-20

FCT-17

Delta-13

Plateau-12

Bauchi-12

Niger-10

Kebbi-9

Ogun-8

Ondo-8

Abia-7

Nasarawa-5

Borno-1

Kwara-1

Benue-1

Anambra-1

Èèyàn 403 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Isinmi

Oríṣun àwòrán, Others

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Eeyan 403 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,082 bayii.

Eeyan 5220 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 420 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Gombe-73

Eko-68

Kano-46

Edo-36

FCT-35

Nasarawa-31

Kaduna-17

Oyo-16

Abia-15

Delta-13

Borno-13

Plateau-8

Niger-7

Rivers-7

Enugu-6

Ogun-6

Kebbi-3

Ondo-1

Anambra-1

Imo-1

Èèyàn 501 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Abámẹ́ta

Eeyan 501 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 15,682 bayii.

Eeyan 5101 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 407 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-195

FCT-50

Kano-42

Kaduna-27

Edo-26

Oyo-22

Imo-21

Gombe-17

Benue-12

Enugu-12

Delta-11

Anambra-11

Ebonyi-10

Nasarawa-9

Ogun-9

Bauchi-8

Kebbi-4

Akwa Ibom-3

Jigawa-3

Katsina-3

Yobe-2

Borno-2

Kwara-1

Ondo-1

Èèyàn 627 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì

Eeyan 627 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi aarun Coronavirus ni Naijiria.

Oríṣun àwòrán, EPA

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 15,181 bayii.

Eeyan 4,891 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 399 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko-229

FCT-65

Abia-54

Borno-42

Oyo-35

Rivers-28

Edo-28

Gombe-27

Ogun-21

Plateau-18

Delta-18

Bauchi-10

Kaduna-10

Benue-9

Ondo-8

Kwara-6

Nasarawa-4

Enugu-4

Sokoto-3

Niger-3

Kebbi-3

Yobe-1

Kano-1

Èèyàn 681 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀

Eeyan 681 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi aarun Coronavirus ni Naijiria.

Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 14,554 bayii.

Eeyan 4,494 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 387 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko -345

Rivers-51

Ogun-48

Gombe-47

Oyo-36

Imo-31

Delta-28

Kano-23

Bauchi-18

Edo-12

Katsina-12

Kaduna-9

Anambra-7

Jigawa-5

Kebbi-4

Ondo-4

Nasarawa-1

Èèyàn 409 míì ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng

Ayẹwo ti fi han pe eeyan 409 mii tun ti ni aarun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ l'Ọjọbọ.

To n tumọ si pe lapapọ, eeyan 13,873 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko arun naa ni Naijiria.

Eeyan 4,351 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 382 ti papoda nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko -201

FCT- 85

Delta- 22

Edo- 16

Nasarawa- 14

Borno- 14

Kaduna- 14

Bauchi-10

Rivers-9

Enugu- 5

Kano- 5

Ogun- 4

Ondo- 4

Bayelsa- 2

Kebbi- 2

Plateau- 2

Èèyàn 663 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun nìkan ṣoṣo

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ti kede eeyan 663 gẹgẹ bi apapọ awọn tuntun mii to ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria lọjọ Iṣẹgun.

NCDC lo fi ikede naa lede loju opo Twitter rẹ, ti apapọ awọn to ti ni arun naa ni Naijiria ti wa di 13464 bayii.

Eeyan 4206 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 365 ti papoda nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko -170

Ogun-108

Bauchi-69

Ebonyi-49

Edo-33

Rivers-30

FCT-26

Jigawa-26

Delta-20

Anambra-17

Gombe-16

Kano-16

Imo-15

Abia-14

Borno-11

Oyo-11

Plateau-8

Kebbi-6

Kaduna-6

Ondo-4

Niger-2

Katsina-2

Osun-1

Ekiti-1

Kwara-1

Nasarawa-1

Èèyà 315 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní ọjọ́ Ajé

Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng

Ajọ NCDC ti kede eniyan 315 gẹgẹ bi apapọ awọn to ni arun Coronavirus lorilẹ-ede Naijiria ni ọjọ Aje.

ANCDC lofi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ, ti apapọ awọn eniyan to ti ni arun naa ti wa da 12801.

Ipinlẹ Eko lo ni eeyan to poju pẹlu eeyan 128 lọjọ Aje nikan soso.

Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ṣe lọ ree:

Lagos- 128

FCT-34

Rivers- 32

Edo- 28

Oyo- 22

Kaduna- 20

Gombe- 13

Ogun- 8

Plateau- 5

Delta- 7

Kwara- 7

Kano- 5

Bauchi- 4

Katsina- 2

Àjọ NCDC kéde èèyàn 260 tuntun míì tó ṣẹṣẹ ni ààrùn Covid-19 ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, Twitter

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Eeyan 260 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi aarun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita lalẹ ọjọ Aiku loju opo Twitter rẹ.

Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 12486 bayii.

Eeyan 3959 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 354 ti dero ọrun nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Abia-67

FCT-40

Eko -38

Ogun-19

Gombe-16

Edo-14

Imo-9

Kwara-8

Katsina-8

Nasarawa-8

Borno-8

Kaduna-6

Bauchi-5

Ekiti-4

Niger-2

Ondo-2

Plateau-2

Kano-2

Sokoto-2

Èèyàn 389 ló tún lùgbàdì àrùn Coronavirus ní ọjọ́ Àbámẹ́ta ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, Twitter

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ti kede eeyan 389 gẹgẹ bi apapọ awọn tuntun mii to ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọ Abamẹta.

NCDC lo fi ikede naa lede loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ, ti apapọ awọn to ti ni arun naa ti wa di 12233 bayii.

Eeyan 3826 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 342 ti papoda nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko -66

FCT-50

Delta-32

Oyo-31

Borno-26

Rivers-24

Edo-23

Ebonyi-23

Anambra-17

Gombe-17

Nasarawa-14

Imo-12

Kano-12

Sokoto-12

Jigawa-8

Ogun-7

Bauchi-5

Kebbi-2

Kaduna-2

Katsina-2

Ondo-2

Abia-1

Niger-1

Èèyàn 328 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus lọ́jọ́ Ẹti ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Ayẹwo ti fi han pe eeyan 328 mii tun ti ni aarun Coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ lọjọ Ẹti.

To n tumọ si pe lapapọ, eeyan 11844 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko arun naa ni Naijiria.

Eeyan 3696 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 333 ti papoda nitori arun ọhun.

Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:

Eko -121

FCT-70

Bauchi-25

Rivers-18

Oyo-16

Kaduna-15

Gombe-14

Edo-13

Ogun-13

Jigawa-8

Enugu-6

Kano-5

Osun-2

Ondo-2

Ènìyàn 350 ló ní àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀

Oríṣun àwòrán, Twitter

Eeyan 350 miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.

Ninu ikede ti Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita ni oju opò ikansiraẹni Twitter wọn ni wọn ti fi lede bẹẹ.

Lapapapọ bayii eeyan 11516 ni ayẹwo fihan pe wọn ti ko arun yii lorilẹede Naijiria bayii.

Eniyan 3535 lo ti ri iwosan gba, nigba eniyan 323 si ti papoda nitori arun Coronavirus.

Bii awọn ipinlẹ naa ṣe lọ ni yii;

Eko-102

Ogun-34

FCT-29

Borno-26

Kaduna-23

Rivers-21

Ebonyi-17

Kwara -16

Katsina-14

Edo-10

Delta-10

Kano-10

Bauchi-10

Bayelsa-9

Imo-8

Plateau-4

Ondo-3

Nasarawa-2

Gombe-1

Oyo-1

Ní Ọjọ́ọ̀rú nìkan, ènìyàn 348 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria

Ajọ NCDC ti kede eniyan 348 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọọru nikan lorilẹede Naijiria.

Oríṣun àwòrán, Others

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 11166.

Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 163 ni Ojo Iṣẹgun nikan soso.

Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3329, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 315.

Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii;

Eko-163

FCT-76

Ebonyi-23

Rivers-21

Delta-8

Nasarawa-8

Niger-8

Enugu-6

Bauchi-5

Edo-5

Ekiti-5

Ondo-5

Gombe-5

Benue-4

Ogun-2

Osun-1

Plateau-1

Kogi-1

Anambra-1

Ènìyàn 241 tuntun ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní Naijiria

Ajọ NCDC ti kede eniyan 241 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Iṣẹgun lorilẹede Naijiria.

Oríṣun àwòrán, Twitter

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 10819.

Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 142 ni Ojo Iṣẹgun nikan soso.

Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3239, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 314.

Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii;

Eko-142

Oyo-15

FCT-13

Kano-12

Edo-11

Delta-10

Kaduna -9

Rivers-9

Borno-8

Jigawa-4

Gombe-3

Plateau-3

Osun-1

Bauchi-1

Ènìyàn 416 ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ajé ní Naijiria

Ajọ NCDC ti kede eniyan 416 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Aje lorilẹede Naijiria.

Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 10578.

Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 192 ni Ojo Aje nikan soso.

Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3122, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 299. Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii;

Eko-192

Edo-41

Rivers-33

Kaduna-30

Kwara-23

Nasarawa-18

Borno-17

FCT-14

Oyo-10

Katsina-7

Abia-5

Delta-5

Adamawa-4

Kano-4

Imo-3

Ondo-3

Benue-2

Bauchi-2

Ogun-2

Niger-1

Ènìyàn 307 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Aiku

Ajọ NCDC ti kede eniyan 307 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Aiku lorilẹede Naijiria.

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 10162.

Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 188 ni Ojo Aiku nikan soso.

Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3007, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 287. Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii;

Eko-188

FCT-44

Ogun-19

Kaduna-14

Oyo-12

Bayelsa-9

Gombe-5

Kano-3

Delta-3

Imo-2

Rivers-2

Niger-2

Bauchi-2

Plateau-1

Kwara-1

Ọjọ́ Satide ni ìgbà àkọ́kọ́ tí ènìyan 553 yóò kó àrùn Coronavirus léékan naa ní Naijiria

Ajọ NCDC ti kede eniyan 553 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Satide lorilẹede Naijiria.

Oríṣun àwòrán, Others

Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 9855.

Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 378 ni Ojo Satide nikan soso.

Eko-378

FCT-52

Delta-23

Edo-22

Rivers-14

Ogun-13

Kaduna-12

Kano-9

Borno-7

Katsina-6

Jigawa-5

Oyo-5

Yobe-3

Plateau-3

Osun-1

Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 2856, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 273.

Ènìyàn 254 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko nìkan ní Ọ̀jọ́ Ẹtì!

Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe awọn to ti ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pe 9,302 bayii.

Oríṣun àwòrán, Twitter/Sanwo Olu

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Eniayn 387 tuntun ni akọsilẹ wa pe o ti ni aarun naa, o si ti wọ ipinlẹ marundinlogoji, ati ilu Abuja.

Ni ipinlẹ Eko nikan, eniyan 254 lo ti lugbadi arun naa ni Ọjọ Eti.

Àkọlé fídíò, May 29: Akala, Aleshinloye sọ̀rọ̀ lórí ọdún kan Seyi Makinde gẹ́gẹ́bíi gómìnà

bayii, eniyan 2697 lo ti ri iwosan gba lọwọ arun Coronavirus, ti eniyan 261 si ti ku nitori arun naa.

Alaye re e lori ipinlẹ ti awọn ẹni tuntun naa ti wa:

Eko-254

Abuja-29

Jigawa-24

Edo-22

Oyo-15

Rivers-14

Kaduna-11

Borno-6

Kano-3

Plateau-2

Yobe-2

Gombe-2

Bauchi-2

Ondo-1

Ènìyàn 182 ni àjọ NCDC kéde pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà

Oríṣun àwòrán, Ncdc

Awọn ti aarun Covid-19 mu l'orilẹ-ede Naijiria ti pọ si, lẹyin ti esi ayẹwo ti ajọ to mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC kede fihan pe eeyan 182 lo tun ti ni aarun naa.

Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii.

Lagos-111

FCT-16

Akwa Ibom-10

Oyo-8

Kaduna-6

Delta-6

Rivers-5

Ogun-4

Ebonyi-4

Kano-3

Plateau-2

Gombe-2

Kebbi-1

Kwara-2

Bauchi-1

Borno-1

Nibayii, eniyan 8915 lo ti ni, 2592 ti ri iwosan, 259 si ti ku.

AWỌN TO NI AARUN COVID-19 NI NAIJIRIA NI 28/05/2020

Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe awọn to ti ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pe 8,733 bayi.

Eniayn 389 tuntun ni akọsilẹ wa pe o ti ni aarun naa, o si ti wọ ipinlẹ marundinlogoji, ati ilu Abuja.

Ni bayii, ipinlẹ Kogi naa ti darapọ mọ awọn ipinlẹ ti aarun naa ti wọ l''orilẹ-ede Naijiria.

Alaye re e lori ipinlẹ ti awọn ẹni tuntun naa ti wa:

Lagos-256

Katsina-23

Edo-22

Rivers-14

Kano-13

Adamawa-11

Akwa Ibom-11

Kaduna-7

Kwara-6

Nasarawa-6

Gombe-2

Plateau-2

Abia-2

Delta-2

Benue-2

Niger-2

Kogi-2

Oyo-2

Imo-1

Borno-1

Ogun-1

Anambra-1

Ṣugbọn, eeyan 2,501 ti ri iwosan, 254 si ti ku.

Skip X post, 5
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 5

AWỌN TO NI AARUN COVID-19 NI NAIJIRIA NI 27/05/2020

Apapọ awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pe ẹgbẹrun mẹjọ ati ojilelọọdunrun le mẹẹrin (8344).

Eyi ri bẹ ẹ lẹyin ti ajọ to n mojuto aarun ni Naijiria, NCDC, tun kede ọrinlerugba din mẹẹrin (276) eeyan to tun ṣẹṣẹ ni lọjọ Iṣẹgun.

Ipinlẹ Eko lo ṣi n lewaju ninu awọn ipinlẹ mẹrinlelọgbọn, ati ilu Abuja, ti aarun naa ti de ni Naijiria.

Skip X post, 6
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 6

Ṣugbọn, ẹgbẹrun meji ati ọrinlelọọdunrun le maarun (2385) eeyan lo ti ri iwosan. Eniyan igba ati mọkandinlaadọta (249) si ti ku.

Eeyan to ti ni aarun coronavirus l'orilẹ-ede Naijiria ti pe ẹgbẹrun mẹjọ ati mejidinlaadọrin bayii.

Eyi ri bẹ ẹ lyin ti ajọ to n gbogun ti aarun ni Naijiria, Nigeria Centre for Disease Control (NCDC) kede esi ayẹwo eeyan igba le mọkandinlọgbọn lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Karun, ọdun 2020.

Skip X post, 7
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 7

Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pọ si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC tun kede okoolelọọdunrun din meje eeyan ti esi ayẹwo wọn ṣẹṣẹ jade.

Ni bayii, eeyan ẹgbẹrun meje, ati ojilelẹgbẹrin din ẹyọkan (7839) ni akọsilẹ wa pa o ti ni aarun naa ni Naijiria.

Akojọpọ awọn ipinlẹ ti esi tuntun naa ti wa niyii.

Skip X post, 8
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 8

Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun l'orilẹ-ede Naijiria, NCDC, kede pe eniyan igba ati marundinlaadọrin ni ayẹwo fihan pe o tun ni aarun coronavirus ni Naijiria.

Ninu esi ayẹwo naa, ipinlẹ Eko ni eeyan mẹtalelaadoje, Oyo ni mẹtalelọgbọn, Edo si ni mejidinlọgbọn.

Awọn ipinlẹ to ku ni:

Skip X post, 9
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 9

Apapọ awọn to ti ni l'orilẹ-ede Naijiria jẹ ẹgbẹrun meje, ati ẹẹdẹgbẹta le mẹrindinlọgbọn (7526).

Ẹgbẹrun meji ati mẹrinlelaadọsan (2174), ti ri iwosan, okoolerugba le ẹyọkan (221) si ti ku.

Esi ayẹwo aarun coronavirus ti ajọ to n gbogun ti aarun ni Naijiria, NDCD, kede ni alẹ ọjọ Ẹti fihan pe eniyan igba ati marundinlaadọta lo tun ti ni aarun naa ni Naijiria.

Ipinlẹ Eko lo ṣiwaju pẹlu mọkanlelaadoje.

Skip X post, 10
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 10

Lọwọlọwọ, eniyan ẹgbẹrun meje ati ọtalerugba le yọkan (7261) lo ti ni Covid-19 ni Naijiria.

Ènìyàn 339 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ọ́bọ̀ ní Nàíjíríà

Eniyan ọọdunrunlemọkandinlogoji lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọọbọ.

Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọọbọ, ni iye awọn to ti ni arun naa ti di ẹgbẹrun meje ati mẹrindinlogun (7016).

NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko, Kano, Oyo, Edo, Katsina, Kaduna, Jigawa, Yobe, Plateau, Abuja, Gombe, Ogun, Bauchi, Nasarawa, Delta, Ondo, Rivers ati Adamawa.

Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni mejeleẹẹdẹgbẹwa (1907), ti ookanlenigba(211) eniyan si ti ku nitori arun naa.

Ènìyàn 284 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́òrú ní Nàíjíríà

Eniyan ọrinlenigbalenimẹrin lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọọru.

Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọọru, ni iye awọn to ti ni arun naa ti le ni ẹgbaata ati ọrinlelẹgbẹtadinmẹta (6677).

NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko, Rivers, Oyo, Abuja, Borno, Plateau, Jigawa, Kano, Abia, Ekiti, Delta, Kwara ati Taraba.

Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni ọgọtadinlẹdẹẹgbẹsan(1840), ti igba eniyan si ti ku nitori arun naa.

Ènìyàn 226 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ Ìṣẹ́gun

Eniyan okoolerugbaolemẹfa lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọ Iṣẹgun.

Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọ Iṣẹgun ni iye awọn to ti ni arun naa ti le ni ẹgbẹẹta ati irinwo(6401).

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko,Ogun, Plateau, Edo,Kaduna,Oyo,Abuja, Adamawa,Jigawa, Ebonyi, Borno, Nasarawa, Bauchi, Gombe, Enugu ati Bayelsa.

Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni ẹẹdẹgbẹsan(1734), ti eniyan mejilelaadọwa si ti ri ku nitori arun naa.

Ènìyàn 216 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ Ajé

Orilẹede Naijiria ti ni eniyan mẹrindinlogunlenigba lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria.

Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọ Aje ni iye awọn to ti ni arun naa ti le ni ẹgbẹẹta(6175).

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko,Katsina, Oyo, Kano, Edo, Zamfara, Ogun, Gombe, Borno, Bauchi, Kwara, Abuja,Kaduna, Enugu ati ipinlẹ Rivers.

Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni ẹgbẹjọ(1644), ti eniyan mọkanlelaadọwa si ti ri ku nitori arun naa.

Ènìyàn 5,162 ló ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà, ti èèyàn 167 sì ti bá ààrùn náà rìn.

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ní àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn ẹ̀tàléláàdọ́wàá to tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn covid-19 ti àpapọ̀ gbogbo ibi tí ǹkan dé dúró ní Nàìjíríà báyìí sì ti di ẹgbẹ̀rún márùn-ún àti méjìlélọ́gọ́jọ.

Ìkéde yìí jẹyọ lójú òpó twitter àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) ní alé ọjọ́bọ.

Àkọlé àwòrán, Ènìyàn 5,162 ló ti ni ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ti èèyàn 167 si ti bá ààrùn náà rìn.
Àkọlé fídíò, U.I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè

Gẹ́gẹ́ bí àjọ NCDC ṣe sọ ènìyàn méjílédinlọ́gọ́ta ló ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ nípínlẹ̀ Eko, mẹ́rìndíláàdọ́ta ni Kano, márùnlélọ́gbọ̀n ni Jigawa àti méjìlá ni Yobe.

Ènìyàn mẹ́sàn-án ni Abuja, nígbà ti méje wáye ni ìpínlẹ̀ Ogun, Plateau àti Gombe ni márùn-ún, mẹ́rìn ní Imo.

Edo, Kwara àti Borno ni èèyàn mẹ́ta, nígbà ti ẹyọ kọ̀ọ̀kan jẹyọ ni Bauchi, Nasarawa àti Ondo.

Ní ojúmọ́ ọjọ́ ẹti yìí, iye ènìyàn to wà lọ́rí àkéte ààrùn Covid-19 jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ta àti ẹgbẹ̀rin lé mẹ́ẹ̀dógún ènìyàn nígbà ti èèyan ẹgbẹ́run kanlélọ́gọ́san ti wà láàlàfíà.

Ní báyìí enìyàn ọgọ́jọléméje ló ti kú látàrí ààrùn Covid-19

Àjọ NCDC kéde èèyàn 184 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 184 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC ti kéde pé ènìyàn mẹ́rinleọgọ́sàn (184) ni àyẹ̀wò tuntun fi hàn pé ó ní ààrùn Covid-19 lórílè-èdè Nàìjíríà ti àpapọ̀ àwọn tó ní ààrùn náà sì tì di ẹgbẹ̀rúnmẹ́rin àti ọ̀rìlélélẹ́ẹ̀gbẹ̀rún o dín mẹ́sàn-án (4971)

Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ ìṣẹ́gun ènìyàn mẹ́rìlélọ́gọ́jọ ló ti kú nígbà ti ẹgbẹ̀rúnkan lé ni ààdọ́rin ti ri ìwòsàn gbà.

NCDC ní, ìpínlẹ̀ Eko ní ènìyàn mọ́kànléláàdọ́ọ́ta, mẹ́tàlélógun ni Jigawa, Kastsina àti Bauchi ni mẹ́rìndílógún nigbàti Kano ni mẹ́rìnlá.

FCT àti Rivers ní mẹ́wàá, nígbà tí ìpínlẹ̀ Kwara ni èèyàn mẹ́sàn-án, ti Delta ati Kaduna ṣe ni márùn-ún, Sokoto ati Oyo ní mẹ́rin, bákan náà ni Kebbi, Nasarawa àti Osun ni mẹ́ta, Ondo si ni èèyàn mẹ́jì.

Ènìyàn kọ̀ọ̀kan ló lùgbàdì àààrùn náà ní Ebonyi, Edo, Enugu Anambra Plateau àti Niger

Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC ti kéde pé ènìyàn mẹ́rìndínláàdọ́jọ ni àyẹ̀wò tuntun fi hàn pé ó ní ààrùn Covid-19 lórílè-èdè Nàìjíríà ti àpapọ̀ àwọn tó ní ààrùn náà sì tì di ẹgbẹ̀rúnmẹ́rinlé ọ̀rìlélélẹ́ẹ̀gbẹ̀rin àti méje (4787)

Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ ìṣẹ́gun ènìyàn mẹ́jìdílọ́gọ́jọ ló ti kú nígbà ti ọ̀tàdilẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀rún-ó-dín-kan (959) ti ri ìwòsàn gbà.

NCDC ní, ìpínlẹ̀ Eko ní ènìyàn mẹ́tàdílọ́gọ́ta, mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n láti Kano, nígbà tí ìpínlẹ̀ Kwara ni èèyàn mẹ́wàá sí, èèyàn Mẹ́sàn ni Edo ní lọ́tẹ̀ yìí.

Ènìyàn mẹ́jọ ló lùgbàdì ààrùn náà ni Bauchi, méje ló tún jẹyọ láti Yobe, Oyo àti Kebbi ni mẹrin, Kastsina àti Niger ni mẹ́ta, Plateau, Borno, Sokoto àti Benue ní méjì nígbà ti Gombe, Ebonyi, Ogun, FCT àti Rivers ní èèyàn kọ̀ọ̀kan

Oríṣun àwòrán, NCDC

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC ti kéde pé ènìyàn ìgbàléméjìlélógójì ni àyẹ̀wò tún fi hàn pé ó ti ní ààrùn Coronavirus lórílè-èdè yìí ti àpapọ̀ àwọn tó ní ààrùn náà Nàìjíríà sì ti di ẹgbẹ̀rún mẹ́rin àti ẹgbẹ̀taléméjílèlógójì.

Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ ajé ènìyàn àádóje ló ti kún nígbà ti èjìlélẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀rún ti ri ìwòsàn gbà.

NCDC ní ìpínlẹ̀ Eko ní ènìyàn mẹ́jìdínláàdọ́rùn, mẹ́rìnlélọ́gọ́ta láti Kano, nígbà tí ìpínlẹ̀ Katsina ni èèyàn mọ́kàndínládọ́ta tí Kaduna si ni mẹ́tàlá

Oríṣun àwòrán, NCDC

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Ènìyàn mẹ́sàn ló tún jẹyọ láti Ogun, nígbà ti mẹ́fà wá lati Gombe, mẹ́rin láti Adamawa ti Abuja sì ní mẹ́ta.

Àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́fà bi Ondo, Oyo, Rivers, Zamfara, Borno, àti Bauchi ní èèyàn kọ̀ọ̀kan

Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC lọ́jọ́ àìkù ti kéde pé ènìyàn ìgbàléméjìdíláàdọ́ta ni àyẹ̀wò tún fi hàn pé o ti ní ààrùn Coronavirus lórílè-èdè yìí ti àpapọ̀ àwọn to ni ààrùn náà ni Nàìjíríà sì ti di ẹgbẹ̀rún mẹ́rin àti mọ́kàndínnírinwó.

Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ ènìyàn tó kú ti n peléke sí, bá ààrùn náà ti mú ẹmi èèyàn mẹ́tàdínlógún lọ lóòjọ́ tí àwọn tó kú sì ti di ọgọ́rùn lé mẹ́tàlélógójì nígbà ti àwọn ọgọ̀rún méje àti mẹ́jìdínlọ́gọ́rin ti gba ìwòsàn lọ́wọ́ ààrùn náà..

Mọ́kanlélọ́gọ́rin àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà wá láti ìpínlẹ̀ Eko, márùndínlógójì láti Jigawa, nígbà tí ìpínlẹ̀ Borno àti Kano ní ènìyàn mẹ́rìndílọ́gbọ̀n.

Ènìyàn ogún ló tún jẹyọ láti Bauchi, nígbà ti mẹ́tàlá wá láti Abuja, méjìla ni ìpínlẹ̀ Edo, mẹ́wàá ní Sokoto àti méje ni Zamfara.

Kwara àti Kebbi ni èèyàn mẹ́rin, Gombe, Taraba, Ogun, àti Ekiti ni èèyàn méji tuntun nígbà ti Osun àti Bayelsa ni ẹnì kọ̀ọ̀kan.

Oríṣun àwòrán, NCDC

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Coronavirus ṣekúpa èèyàn mẹrin l'Abuja, méjì ní Kebbi, ẹni márùnlélógójì jàjàbọ́- NCDC

NCDC update on coronavirus: Covid-19 ṣekúpa èèyàn mẹrin l'Abuja, méjì ní Kebbi, ẹni márùnlélógójì jàjàbọ

Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng

Aarun coronavirus ti ṣekupa eeyan mẹrin ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi ọrọ naa mulẹ loju opo Twitter rẹ.

Ninu akọsilẹ ajọ naa lori ọrọ covid-19 fun ọjọ Abamẹta, eeyan marunlelogoji lo jajabọ lọwọ aarun naa ti wọn si ti pada sile wọn.

O di eeyan mẹjọ ti coronavirus ti pa niluu Abuja bayii.

Kii ṣe ilu Abuja nikan ni coronavirus ṣọṣẹ lọjọ Abamẹta, eeyan meji lo gbẹmi mi ni ipinlẹ Kebbi nigba ti eeyan kọọkan ki nipinlẹ Bornu, Katsina, Kaduna, Kwara ati Nasarawa.

Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC

Lapaapọ, eeyan mọkanla laarun covid-19 pa lọjọ Satide kaakiri Naijiria gẹgẹ bi akọsilẹ.

Ìjọba orílẹ̀-èdè Naijiria tí kéde àwọn ènìyàn tuntun tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ kó ààrùn coronavirus, ní báyìí, ènìyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́rin lé ni ọ̀kànléláàdọ́jọ (4151) to ti ni ààrùn náà ni Nàìjíría.

Àjọ to n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lọ́rílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NCDC) kéde lórí àtẹjísẹ́ wọ́n lálẹ́ ọjọ́ sátide lo fi ìkéde náà síta.

Oríṣun àwòrán, NCDC

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Gẹ̀gẹ́ bí àjọ náà ṣe sọ, ẹ̀nìyàn mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn-ún (97) lo lùgbàdì àarùn náà ni ìpínlẹ̀ Eko, mẹ́rìnlélógójì (44) ni Bauchi, mọ́kàndínlọ́gbọ̀n (29) ní Kano àti mọ́kàndílógún (19) ni Katsina.

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Ìpínlẹ̀ Borno ni mẹ́tàdínlógun (17), Abuja ènìyàn méje (7), Kwara mẹ́fà (6), Oyo márùn-ún (5) nígbà tí Sokoto àti Adamawa ni ènìyàn mẹ́ta-mẹ́ta.

Kebbi, Ogun àti Plateau ni ènìyàn méjì-méjì nígbà tí Ekiti ni ènìyàn kan soso.

Láti ìgbà ti ààrùn náà ti bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ kẹtàdílọ́gbọ̀n oṣù keji ẹdún 2020, ni o tí tàn kálẹ̀ si ìpínlẹ̀ mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n àti Abuja báyìí.

Ìpínll Eko náà si ni ìpínlẹ̀ to o ni ènìyàn to pọ̀ jù nítórí ibẹ̀ ni a ti rí ẹni àkọ́kọ́, ènìyàn to lé ní ẹgbẹ̀run kan abọ ló ti ni ààrùn náà ni ìpínlẹ̀ Eko, Ipinlẹ Kano lo tèlé, pẹ̀lú ènìyàn ọgọ́rùn márùn lé mẹ́rìndinlọ́gọ́rin, lẹ́yìn náà ni Abuja to ti ni ènìyàn ọ̀ọ̀dúnrún lé mẹ́tàlélógójì.

Oríṣun àwòrán, NCDC

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Oríṣun àwòrán, NCDC

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 386 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Èsì àyẹ̀wò àwọn ènìyàn to ni ààrùn Corornavirus fi hàn pé ènìyàn ọ̀ọ̀dùrún lémẹ́rìdíláàdọrun lo tún ti lùgbàdì àrùn náà.

Alẹ́ ọjọ́ ẹti ni ikéde yìí jáde, tí ìpínlẹ̀ Eko si ní iye èèyàn to pọ̀ jùlọ pẹ̀lúu èèyàn mẹ́ràndín ni ààdọ́san, ]ipínlẹ̀ Kano ṣe ipo keji, pẹ̀lú èèyàn márùndinlọ́gọ́ta.

Kastina ni èèyàn mọkanlelọ́gbọ̀n, Abuja ní Ogun, Borno mẹ́tadinlogun, Bauchi mẹẹdódogún, Nasarawa mẹ́rìnlá, Ogun mẹ́tàlá àti Plateau pẹlú èèyàn mẹ́wàá.

iyé èèyàn túntun to lùgbàdì àrùn náà ni àwọn ìpińlẹ̀ makànlá tókù kò tó márùn-márùn.

Skip X post, 11
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 11

Ní bayìí èèyàn ẹgbẹ̀run mẹ́rin din díẹ̀ (3912) lo ti lùgbàdì à[rùn Coronavirus ní Nàìjíríà.

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 386 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà

Àjọ NCDC kéde ènìyàn 381 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà

NCDC update on coronavirus: Àjọ NCDC tún ti kéde ènìyàn 381 tó ní Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà

Àkọlé àwòrán, Èèyàn 5 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria

Esi ayẹwo aarun Covid-19 tun ti fihan pe eeyan ọrinlelọọdunrun o le ẹyọkan lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.

Alẹ Ọjọbọ ni ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede eyi lori ayelujara Twitter rẹ.

Skip X post, 12
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 12

Lọwọlọwọ, ẹgbẹrun mẹta ati ẹẹdẹgbẹta le mẹẹrindinlọgbọn (3526) eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.

Oríṣun àwòrán, Ncdc

Àjọ NCDC kéde ènìyàn 195 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà.

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe esi ayẹwo Covid-19 ti fihan pe igba din maarun eeyan lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.

Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:

Skip X post, 13
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 13

O ti pe ẹgbẹrun mẹta ati marundinlaadọjọ eeyan to ti ni aarun yii ni Naijiria. Ipinlẹ Eko lo ṣi n le waju.

Àkọlé àwòrán, Aworan afikun iroyin nipa ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria

Ni bi a ṣe n sọrọ iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe on laarun coronavirus lorilẹede Naijiria ti ẹgbẹrun mẹta o dun aadọta eeyan bayii.

Ajọ NCDC lo ṣalaye ẹkunrẹrẹ eyi ninu ikede alaalẹ ti wọn maa n ṣe lati sọ ibi ti iṣẹ de duro lori ọrọ ajakalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria.

Àkọlé àwòrán, Aworan afikun iroyin nipa ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria

Atupalẹ onka iye awọn to ti ni aarun naa, iye awọn to n gba itọju lọwọ, iye awọn to ti ri iwosan ati awn ti arun naa ti ran lọ si ọrun niyi ninu atẹ tabili yii.

Àkọlé àwòrán, Aworan afikun iroyin nipa ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria

Ipinlẹ Eko lo n lewaju loke tente ni iye awsn to ti ni arun naa. Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn onimọ n jẹ ko di mimọ pe o ṣeeṣe ko jẹ wi pe nitori pe ipinlẹ Eko ni eto ayẹwo rẹ pọ juls lo fa eyi bakan naa ni ipinlẹ Kano naa ti goke tẹlee pẹlu ibẹrẹ eto ayẹwo nibẹ lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye to wọ tọ iku ọwọọwọ ati aisi itọju ati amojuto to peye fun ajakalẹ arun naa nibẹ.

Coronavirus in Nigeria: Àjọ NCDC tún ti kéde ènìyàn 148 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà

Esi ayẹwo aarun Covid-19 tun ti fihan pe eeyan mejidinlaadọjọ lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.

Alẹ ọjọ Iṣẹgun ni ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede eyi lori ayelujara Twitter rẹ.

Skip X post, 14
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 14

Ni bayii apapọ eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria jẹ ẹgbẹẹdogun din aadọta.

Akojọpọ rẹ re e:

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe esi ayẹwo Covid-19 ti fihan pe ojilerugba le maarun eeyan lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.

Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:

Skip X post, 15
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 15

Ni bayii, ẹgbẹrun meji ati ẹgbẹrin le meji (2802) eniyan lo ti ni aarun naa ni Naijiria.

Ènìyàn 170 tún ti ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria ti kede pe esi ayẹwo ti fihan pe aadọsan eeyan lo tun ti ni aarun Covid-19 l'orilẹ-ede Naijiria.

Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:

Skip X post, 16
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 16

Ni bayii, ẹgbẹrun meji ati ọtalelẹẹdẹgbẹta (2558) eniyan lo ti ni aarun naa ni Naijiria.

Àjọ NCDC tún ti kéde èèyàn 220 míràn tó ní Coronavirus ní Nàìjíríà

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria ti kede pe esi ayẹwo ti fihan pe okoolelọdunrun eeyan lo tun ti ni aarun Covid-19 l'orilẹ-ede Naijiria.

Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:

Lagos - 62

FCT - 52

Kaduna 31

Sokoto 13

Kebbi - 10

Yobe - 9

Borno - 6

Edo - 5

Bauchi - 5

Gombe - 4

Enugu - 4

Oyo - 4

Zamfara - 3

Nasarawa - 2

Osun - 2

Ebonyi - 2-

Kwara - 2

Kano -2

Plateau - 2

Lọwọlọwọ, o ti pe ẹgbẹrun meji ati irnwo din mejila (2388) eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.

Eniyan 238 tun ti ni Coronavirus ni Naijiria

Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni orilẹ-ede Naijiria, NCDC tun ti kede esi ayẹwo ojilerugba din meji eniyan to tun ti ni aarun Covid-19.

Bi esi tuntun naa ṣe lọ niyii:

92-Kano

36-FCT

30-Lagos

16-Gombe

10-Bauchi

8-Delta

6-Oyo

5-Zamfara

5-Sokoto

4-Ondo

4-Nasarawa

3-Kwara

3-Edo

3-Ekiti

3-Borno

3-Yobe

2-Adamawa

1-Niger

1-Imo

1-Ebonyi

1-Rivers

1-Enugu

Lọwọlọwọ, o ti pe ẹgbẹrun meji le aadọsan eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.

Èèyàn 204 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa

Eeyan mẹrinlenigba miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.

Ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita lọjọru, ọgọrin ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Kano, mẹrundinlaadọta ninu wọn wa lati ilu Eko, mejila ninu wọn wa lati ilu Gombe, mẹsan ninu wọn wa lati Bauchi ati Sokoto.

Meje lati Borno ati Edo, mẹfa lati Rivers ati Ogun,mẹrin ni ilu Abuja, Akwa Ibom ati Bayelsa, mẹta ni ilu Kaduna, meji ni ilu Oyo, meji ni Delta ati Nazarawa, ẹyọkan ni Ondo ati Kebbi.

Lapapapọ bayii ẹgbẹwadinmejidinladọrin (1932) eeyan ni ayẹwo fihan pe wọn ti ko arun yii lorilẹede Naijiria bayii.

Èèyàn 196 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa

Eeyan mẹrindinlọgọfa miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.

Ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita lọjọru, mẹtadinlaadọrun ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko, mẹrinlelogun wa lati ipinlẹ Kano, Gombe ni mejidinlogun, Kaduna mẹtadinlogun bẹẹni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja naani mẹrindinlogun.

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Lapapapọ bayii okoolelẹẹdẹgbẹrin ati mẹjọ (1728) eeyan ni ayẹwo fihan pe wọn ti ko arun yii lorilẹede Naijiria bayii.

Katsina mẹwaa, Sokoto mẹjọ, Ẹdo meje, Borno mẹfa, Yobe, Ebọnyi ati Adamawa si ni ẹyọ kọọkan

Coronavirus cases in Africa: Èèyàn 195 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa

Eeyan marundinigba miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.

Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, ọgọrin ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mejidinlogoji wa lati ilu Kano.

Bakan naa ni mẹẹdogun lati ilu Ogun, mẹẹdogun ni ilu Bauchi, mọkanla ni Borno, mẹwa ni Gombe, mẹsan ni Sokoto, marun un ni Edo, marun un ni Jigawa, meji ni Zamfara, ẹyọkan ni Rivers, ẹyọkan ni Enugu, ẹyọkan ni Delta, ẹyọkan ni FCT ati ẹyọkan ni Nasarawa.

Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹmejilelaadọtadinlẹgbẹjọ.

Eniyan marundinlọgọtalenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn mẹrinlelogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.

Èèyàn 64 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa

Eeyan mẹrinlegọta miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.

Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, mẹtalelọgbọn ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mẹẹdogun wa lati ilu Abuja, mọkanla lati ilu Borno ati meji ni ilu Gombe.

Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹtalelọgọtadinlẹgbẹfa

Eniyan marundindinlọgọtalenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn ogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.

Èèyàn 91 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa

Eeyan mọkanlelaadọrun miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.

0Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, mẹtalelogoji ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mẹjọ wa lati Sokoto, mẹfa lati Taraba, marun un ni Kaduna, marun un ni Gombe, mẹta ni Ondo, mẹta ni ilu Abuja.

Bakan naa ni wọn kede pe mẹta wa ni ilu Edo, mẹta ni Oyo, mẹta ni Rivers, mẹji ni Osun, ẹyọkan ni Akwa Ibom, ẹyọkan ni Bayelsa, ẹyọkan ni Ebonyi, ẹyọkan ni Kebbi.

Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹgbẹrunlenigbalemẹtalelaadọrin.

Eniyan mọkanlelogojilenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn ogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.

Èèyàn 78 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa

Eeyan mejidinlọgọrin miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.

Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, mẹtalelọgbọn ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mejidinlogun wa lati ilu Borno, mejila ni ilu Osun, mẹsan ni ilu Katsina, mẹrin ni ilu Kano, mẹrin ni ilu Ekiti, mẹta ni ilu Edo, mẹta ni Bauchi, ẹyọkan ni Imo.

Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹgbẹrunleniejilelọgọsan.

Eniyan mejilelokolenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn marundinlogoji ti filẹ ṣaṣọ bora.

Èèyàn 114 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa

Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC lo fi ikede naa si kita loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Skip X post, 17
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 17

Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹgbẹrunleọkandinlọgọrun un.

Eniyan mẹjọlenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn mejilelọgbọn ti filẹ ṣaṣọ bora.

Èèyàn mẹ́wàá tún ti ṣẹ́gun Coronavirus l'Eko àkéte

Gomina ipinlẹ Eko, babajide Sanwo-Olu ti kede iroyin ays eleyi to ni eeyan mẹwaa miran ti ruula lọwọ arun Coronavirus l'Eko akete.

Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu

Gomina Sanwo-Olu ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe mẹta ninu awọn eeyan wọnyii lo jẹ obinrin ti meje yooku si jẹ Ọkunrin.

Mẹẹta ninu ọkunrin atobinrin mẹwaa ti wọn ri iwosan l'Eko yii ni wọn jẹ ọmọ ilẹ okeere.

Gomina Sanwo-Olu ni ko si aniani pe iye awọn to n ni arun naa n peleke sii, sibẹ iroyin aṣeyọri itọju awọn wsnyii n fihan pe iroyin ibanujẹ nikan kọ lo sodo si ọrs arun naa bayii.

Sibẹ o rọ awọn eeyan ipinlẹ Eko lati maṣe jafara pẹlu eto imọtoto wọn o nitori o daju pe iṣẹgun n bọ laipẹ.

Bakan naa lo rọ gbogbo eeyan lati darapọ mọ eto ikede 'wọ ibomu rẹ l'Eko' iyẹn '#MaskUpLagos campaign'

Nàìjíríà tún ní àkọsílẹ̀ ènìyàn 108 tó ní ààrùn coronavirus

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC tun ti kede pe esi ayẹwo fihan pe eniyan mejidinlaadọfa lo tun ti ni coronavirus ni Naijiria.

Mejidinlọ̀gọ̀rin lara awọn eeyan naa lo wa lati ipinlẹ Eko, mẹrila si wa lati ilu Abuja.

Lọwọlọwọ, o ti pe ẹgbẹrun kan din mẹsan to ti ni aarun naa ni Naijiria.

Atupalẹ awọn to ku niyii:

Skip X post, 18
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 18

Ó ti pé ènìyàn 981 tó ní Coronavirus ní Nàìjíríà báyìí

Wọn tun ti ri eniyan mọkanlelaadọrun to ni aarun coronavirus ni Naijiria.

Ajọ NCDC kede eyi lalẹ Ọjọru.

Lọwọlọwọ, o ti pe ọrinlelẹgbẹrin din meje eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.

Àkọlé fídíò, Òǹtàjà aṣọ ni mí tẹ́lẹ̀, ọ̀dá owó ló sọ mi di alábárù

Eniyan igba din mẹta ti ri iwosan, mejidinlọgbọn si ti ku.

Atupalẹ awọn ipinlẹ ti wọn ti ri ikọọkan awọn to ṣẹṣẹ ni re e.

Skip X post, 19
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 19

Àjọ to n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Naijiria NCDC ti kéde ènìyàn ogún àwọn ènìyàn míràn to ti ni ààrun Corornavirus lórílẹ̀-èdè Naijiria.

Mẹ́tàlá nínú rẹ̀ jẹ láti ìpiínlẹ̀ Eko, méjì wá láti Edo, méjì láti Kano, meji láti ogun nígbà ti ẹyọkan jẹ lati Ondo.

Ní bayii o ti di ènìyàn òjìlélọ́ọ̀dúnrun àti mẹta to ti ni ààrun coronavirus ni Naijiria, ẹniyan mọ́kànléláàdọ́rún ló ti gba ìtúsill lọ́wọ́ ààrun náà ti ènìyàn mẹ́wàá si ti ba ààrun náà lọ

Ipinlẹ mọkandínlogun ni ààsùn náà de dúró.

Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 325 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria báyìí

Àkọlé àwòrán, Èèyàn 5 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria

Ènìyàn márùn míràn ni àyẹwò NCDC fi han pe o tu ti ni ààrun Coronavirus lórílẹ̀-èdè Naijiria bayii.

Nínú márùn-un yìí, méjì nínú wọn yìí jẹ́ láti ipinlẹ Eko, meji ni ìpínlẹ̀ Kwara, ẹyọkan ni ipinlẹ Katsina

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ lalẹ ọjọ Aikú.

Ní bayíì, ènìyàn marunlélọ́gọ́rin ló ti ri ìwòsàn ti wọ́n si ti lọ ilé wọ́n nígbà ti iye ènìyàn to kú kò tíle ni mẹ́wàá

Ẹ̀wẹ̀, ìpínlẹ̀ makandinlogun lo ti kéde ààrun Coronavirus bayii lórilẹ̀-èèdè Naijiria.

Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 318 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria báyìí

Àkọlé àwòrán, Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 318 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria báyìí

Ènìyàn mẹ́tàlá míràn ni àyẹwò NCDC fi han pe o tu ti ni ààrun Coronavirus lórílẹ̀-èdè Naijiria bayii.

Nínú mẹ́tàlá yìí, Mọkanla nínú àwọn mẹtala yìí jẹ́ láti ipinlẹ Eko, ẹyọkan ni ìpínlẹ̀ Delta, ẹyọkan ni ipinlẹ Kano

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ lalẹ ọjọ Ẹti.

Ní bayíì, ènìyàn ààdọrin ló ti ri ìwòsàn ti wọ́n si ti lọ ilé wọ́n nígbà ti àwọn mẹ́wàá ti baa ààrun náà lọ

Okòólélọ́dúnrun àti mẹta ènìyàn lo ti ni àrun náà ni Naijiria gẹ́gẹ́ bi NCDC se sọ

Ẹ̀wẹ̀, ìpínlẹ̀ mọ́kandinlogun àti Abuja lo ti kéde ààrun Coronavirus náà bayii lórilẹ̀-èdè Naijiria.

Èèyàn 17 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria

Eeyan mẹtadinlogun miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun coronavirus bayii.

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ lalẹ ọjọ Ẹti.

Nipa bayii, eeyan marunlelọọdunrun ni iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.

Mẹjọ ni ilu Eko, Mẹta ni ipinlẹ Katsina, Meji nilu Abuja, ẹyọkan ni ipinlẹ Niger, Kaduna, Anambra, ati Ondo

Iye awọn to ti ri iwosan kuro lọwọ arun yii ti gbera sọ di mejidinlaadọta, ti eeyan meje miran si ti jade laye.

Èèyàn 14 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria

Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹrinla miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.

Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọbọ.

Wọn ni eniyan mẹtala miiran tun ti lugbadi aarun naa ni ipinlẹ Eko ati ẹyọkan ni ipinlẹ Delta.

Apapọ gbogbo eeyan to ni aarun covid 19 ni Naijiria bayii jẹ mejidinlaadọrunlenigba.

Èèyàn 22 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria

Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mejilelogun miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.

Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọru.

Wọn ni eniyan mẹẹdogun miiran tun ti lugbadi aarun naa ni ipinlẹ Eko, mẹrin ní Abuja, meji ni Bauchi, ẹyọkan ni ipinlẹ Edo.

Apapọ gbogbo eeyan to ni aarun covid 19 ni Naijiria bayii jẹ ọrin le lugba o din mẹrin.

Èèyàn 16 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria

Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹe miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.

Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọ Iṣẹgun.

Wọn ni eniyan mẹwa ni ipinlẹ Eko, méjì ní Abuja, meji ni Oyo, ẹyọkan ni Delta ati ẹyọkan miran ni Katsina.

Ni apapọ ẹniyan mẹrinlelaadọtalenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan mẹrinlelogoji si ti ri iwosan gba, amọ ti ẹniyan mẹfa si ti ku.

Èèyàn mẹ́fà míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria

Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹfa miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.

Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọ Aje.

Wọn ni eniyan meji ni ipinlẹ Kwara, méjì ní Edo, ẹyọ kọ̀ọ̀kan ní ipinlẹ Rivers àti Abuja.

Ni apapọ ẹniyan mejidinlogojilenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan marundinlogoji si ti ri iwosan gba, amọ ti ẹniyan marun si ti ku.

Èèyàn mẹ́jọ míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria

Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹjọ miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.

Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni Ọjọ Isinmi.

Wọn ni eniyan marun un ni ilu Eko, eniyan kan ni ilu Kaduna ati eniyan meji ni olu ilu Naijiria, Abuja.

Ni apapọ ẹniyan mejilelọgbọnlenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan mẹtalelọgbọn si ti ri iwosan gba, amọ ti ẹniyan marun si ti ku.

NCDC ti kede pe eniyan marun un miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria

Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan marun un miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.

Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni Ọjọ Satide.

Skip X post, 20
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 20

Wọn ni eniyan mẹta ni ilu Bauchi ati eniyan meji ni olu ilu Naijiria, Abuja.

Skip X post, 21
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 21

Ni apapọ ẹniyan mẹrinlenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan mẹẹdọgbọn ri si ti gba iwosan, amọ ti ẹniyan mẹrin si ti ku.

Eeyan mẹrin miran tun ti ruu la lọwọ arun Coronavirus.

Iroyin ayọ miran ree lori ọwọja arun Coronavirus to n waye bayii.

Ni ipinlẹ Eko, eeyan mẹrin miran tun ti ruu la lọwọ arun Coronavirus.

Commissioner feto ilera, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo kede iroyin ays yii nibi apero pẹlawọn akọroyin to ṣe lọjọ Ẹti.

Ṣaaju ọjọ Ẹti, eeyan mọkandinlogun ti ri iwosan kuro lọwọ arun naa.

Coronavirus in Osun: Ènìyàn mẹ́fà míràn ní àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe awọn tun ti ṣawari eeyan mẹfa miran to ni arun Coronavirus ni ipinlẹ Ọṣun.

Ajọ naa fi sita loju opo twitter rẹ pe pẹlu bo ṣe ri yii, o ti di aadọwa eeyan ti wọn ti ṣawari pe o ni arun naa bayii lorilẹede Naijiria.

Ogun eeyan ni wọn ti gba iwosan lọwọ yii ti eeyan meji si ti jade laye.

Ni ipinlẹ Ọṣun nikan, apapọ iye awọn to ti ni arun naa bayii ti di ogun.

Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́wàá míì tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria

Eeyan mẹwa miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.

Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo twitter rẹ ṣalaye pe, meje ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, ati mẹta ni Abuja.

Skip X post, 22
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 22

Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di mẹrinlelọgọsan an.

Ogun ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn awọn meji ti filẹ ṣaṣọ bora.

Àkọlé fídíò, Ṣé fífi òrí pa ọwọ́ rẹ leè dáàbò bò ọ́ lọ́wọ́ Coronavirus?

Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 23 míì tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Eniyan mẹtalelogun miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.

Ileeṣẹ ijọba to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ lalẹ Ọjọru.

Skip X post, 23
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 23

Mẹsan an ninu awọn eeyan ọhun wa ni ipinlẹ Eko, meje wa ni Abuja, marun un ni ipinlẹ Akwa Ibom, ẹnikan ni Kaduna ati ẹnikan yoku ni Bauchi.

Ni bayii, eeyan mẹrinlelaadọsan an (174) lo ti lugbadi arun naa ni Naijria, awọn mẹsan an ti gbawosan, ti eeyan meji lara wọn si ti jẹ Ọlọrun nipe.

Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ṣé ọtí leè dènà tàbí pa àrùn Coronavirus bi?

Coronavirus in Nigeria: Àwọn alárùn Coronavirus l'Eko gbé fídíò síta láti ṣí aráàlú létí

Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Àwọn alárùn òrónà l'Eko gbé fídíò síta láti ṣí aráàlú létí

Awọn eeyan kan ti wọn ti ko arun COVID-19 ti wọn wa ni ibudo iwosan ajakalẹ arun IDH ni Yaba nilu Eko ti gbe fidio kan sita lati ṣe itaniji fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria ati lati fi ẹmi imoore han si awọn olutọju wọn nibẹ.

Fidio ọhun ti wọn fi sita loju opo ayelujara lọjọru ṣe afihan awọn to ni arun naa pẹlu akọle lorisirisi lọwọ wọ iboju ninu fidio naa.

Lara awọn ohun ti wọn kọ sara iwe alakọle ti wọn gbe sọwọ ni "Ootọ ni arun COVID-19"

"Adupẹ fun awọn eleto ilera to n tọju wa" ati bẹẹbẹẹ lọ

Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn mẹ́sàn án l'Ọ́ṣun, méjì l'Edo, Ẹ̀yọkan l'Ékìtì kó Coronavirus

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Eeyan mejila miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.

Atẹjade kan eleyii ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria fi sita loju opo twitter wọn ṣalaye wi pe eeyan mẹsan ninu awsn ti ayẹwo ṣẹṣẹ fi han naa lo wa ni ipinlẹ Ọṣun, meji wa ni ipinlẹ Edo, Ẹyọkan toku si wa lati ipinlẹ Ekiti.

Eyi ti sun iye awọn to ni arun yii siwaju di mọkanlelaadọjọ, 151.

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Coronavirus in Nigeria: èyàn 178,000 tó kó ààrùn Coronavirus ti rí ìwòsàn lágbáyé

Ìròyìn tó ń jáde láti fásitì Johns Hopkins tó wà l'Amerika, fasiti tó ń ṣe ìwádìí nípa nǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ lórií ààrùn Coronavirus, ti fi hàn pé ó kéré jù èèyàn 178,378 tó ní ààrùn Coronavirus tẹ́lẹ̀ ni wọ́n ti rí ìwòsàn .

Báyìí ni ọ̀rọ̀ yìí ṣe rí ní òwúrọ̀ Ọjọ́bọ, ọjọ́ kínní oṣù kẹẹ̀rin , ọdún 2020.

Fásitì náà sọ pé, èèyàn tó kó ààrùn ààrùn Coronavirus lágbáyé ju eeypan 860,000 lọ, nígbà tí ààrùn ná ti pa èèyàn 42,354.

Orílẹ̀èdè mẹ́wàá tí àjàkálẹ̀ ààrùn náà ti pọ̀ ni :

Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́rin míràn ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.

Ijọba apapọ ti kede pe eeyan mẹrin miran ti ni aarun coronavirus ni Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.

Mẹta ninu awọn eeyan ọhun wa ni Abuja ti ẹnikan to ku si wa ni ipinlẹ Eko.

Nibi ọrọ de duro bayi, eeyan mọkandinlogoje (139) lo ti fara kaasa arun na lorilẹede yii, awọn meji lara wọn ti jẹ Ọlọrun nipe, ti mẹsan an si ti ri iwosan.

Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Skip X post, 24
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 24

Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́ta ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, ẹyọkan l'Ógùn tún ti kó àrùn Coronavirus

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria tun ti kede eeyan mẹrin miran pẹlu arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.

Mẹta ninu awọn eeyan naa lo wa lati ipinlẹ Ọṣun, eeyan kan yooku si wa lati ipinlẹ Ogun.

Eyi ti sọ iye awsn eeyan ti wọn ti kede pẹlu arun naa bayii di marundinlogoje, (135)

Meji ninu wọn lo si ti jade laye.

Ni alẹ ọjọ aje ni ajọ yii kede ogun eeyan miran to ti ko arun naa.

Mẹtala ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko, mẹrin lati Abuja, meji lati ipinlẹ Kaduna ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde si kun iye wọn.

Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn márùn ún bọ́ lọ́wọ́ ìgbèkùn àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Èkó

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Eniyan marun un miran tun ti gba iwosan lẹyin ti wọn gba itọju fun arun coronavirus.

Oluranlọwọ fun aarẹ Muhammadu Buhari, Bashir Ahmad lo fi lede bẹẹ loju opo ikansiraẹni Twitter.

Minisita feto ilera pẹlu ti fi idi rẹ mulẹ nibi ifọrọwerọ to ṣe pẹlu awọn oniroyin ni ọsan oni.

Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ìjọba London ti da ọlọ́pàá sí ìgboro láti mú ẹni tó bá ń rìn gbéregbère

Iye awọn ti wọn ti gba itoju bayii ti di mẹjọ.

Amọ Lọwọlọwọ bayii, o ti le ni ọgọrun un eniyan to ti ni arun Coronavirus naa lorilẹede Naijiria.

Coronavirus Update: Èèyàn mẹ́sàn án míràn tún ni Coronavirus nípìnlẹ́ Eko, ó di èèyàn 111 tó níi ní Nàìjíríà

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Eniyan mẹrinla miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita lalẹ ọjọ Aiku loju opo Twitter rẹ.

Mẹsan an ninu awọn eeyan ọhun wa ni ipinlẹ Eko, ti awọn marun un to ku si wa ni Abuja.

Skip X post, 25
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 25

Nibi ọrọ de duro bayi, eeyan mọkanlelaadọfa (111) lo ti lugbadi arun na lorilẹede yii, ti ẹnikan si ti jẹ Ọlọrun nipe.

Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe "hand sanitizer" nínú ilé yín

Corona in Nigeria: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun gbé àgádágodo sẹ́nu ibodè rẹ̀ tóri àrùn Coronavirus

Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR

Àkọlé àwòrán, O nio jẹ ọna lati ṣadinku ba kiko arun Coronavirus wọ ipinlẹ ọhun lati awọn ipinlẹ bi ipinlẹ Eko

Ijọba ipinlẹ Ogun, labẹ iṣakoso Gomina Dapo Abiodun ti pasẹ pe ki wọn ti gbogbo ibode to wọ ipinlẹ naa lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.

Gomina Abiodun sọ loju opo Twitter rẹ pe igbesẹ naa jẹ lati ṣadinku ba kiko arun Coronavirus wọ ipinlẹ ọhun lati awọn ipinlẹ to yi ka, papa julọ ipinlẹ Eko.

Igbeṣe yii ni yoo bẹrẹ lati aago mejila orun, ọjọ Aiku, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹta ọdun 2020.

Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus
Skip X post, 26
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 26

Eyi n tumọ si pe ko ni si aye lati wọle tabi jade kuro ni ipinlẹ naa lasiko yii.

Abiodun sọ pe "Mo ti paṣẹ ki wọn ti gbogbo ibode to wọ ipinlẹ yii lati awọn nipinlẹ to yi wa ka ati awọn orilẹ-ede mii."

Skip X post, 27
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 27

Abiodun tẹsiwaju pe ki awọn eeyan ipinlẹ naa fọwọsowọpọ pẹlu ijọba oun lati gbogun ti ajakalẹ arun naa to n ba gbogbo agbaye finra.

O ni ijọba ọun yoo ma ṣatunyẹwo igbesẹ naa ni igba de igba titi ti ọrọ ajakalẹ arun ọhun yoo fi niyanju.

Àkọlé fídíò, Njẹ Chloroquine nipa kankan lati le koju Coronavirus

CoronaUpdate: Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna,Nasir El Rufai nàá ti ní àrùn Coronavirus

Oríṣun àwòrán, @elrufai

Gomina ipinlẹ Kaduna Nasir El Rufai ti kun awọn Gomina to lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.

Loju opo Twitter rẹ ni o fi ikede yi si ninu fọnran fidio kan ti o ti kede fawọn eeyan ipinlẹ rẹ.

O ni irọle ọjọ Abamẹta ni oun fi ara oun silẹ fayẹwo amọ bayi esi ti fi han pe oun ni Coronavirus.

Skip X post, 28
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 28

Gomina El Rufai ni igbakeji oun yoo ma dari gbogbo eto nipa kikoju Coronavirus lasiko ti oun ba wa ni ayẹwo.

Ko sọ ibi ti oun ti koarun naa ṣugbọn o ni ki gbogbo awọn eeyan ipinlẹ rẹ duro nile ki wọn si tle ilana didaabo bo araẹni lọwọ Coronavirus

Coronavirus ti mu èèyàn 1 ní Benue, èèyàn 7 mìíràn ní Eko

Ipinlẹ Benue ti di ipinlẹ tuntun ti yoo gbalejo arun Coronvirus ni Naijiria pẹlu bi ijọba ti ṣe kede pe eeyan kan ti ni arun naa nibẹ.

Gomina Samuel Ortom sọ ọrọ yi fawọn akọroyin lọjọ Abamẹta.

Oríṣun àwòrán, GovSamuelOrtom

Yatọ si ikede ijọba yi, ajọ to n mojuto itankalẹ arun ni Naijiria NCDC naa fi si oju opo wọn pe eeyan meje miran naa ti ko aisan naa nilu Eko.

Pẹlu iye eeyan tuntun ti wọn kede l'Eko ati Benue, apapọ iye eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria ti di mọ́kàndínláàdọ́rùn ún.

Skip X post, 29
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 29

Ṣaaju lati fi to yin leti pe eeyan mọkanla miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria, eleyii ti apapọ awọn to ni arun naa fi da mọkanlelọgọrin.

Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC lo fi iroyin yin lede ni oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.

Skip X post, 30
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 30

NCDC ni eniyan mẹjọ miran lo lugbadi arun naa ni ipinlẹ Eko, meji ni ipinlẹ Enugu ati ẹyọkan ni ipinlẹ Edo.

Lati igba ti ajakalẹ arun yii ti de orilẹede Naijiria, eniyan kan lo ti ku nitori arun naa, ti ile iwosan si ti fi awọn mẹta silẹ lẹyin ti wọn bori arun naa.

Àkọlé fídíò, Coronavirus: Kò sí ẹni tí coronavirus kò le mú

Ajọ NCDC tun ṣe atupale awọn ipinlẹ ti arun Coronavirus naa ti tan de.

Skip X post, 31
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 31